Iná sọ Ọjà Òkìtìpupa di Eérú
Ìjàm̀bá iná àjóòkú kan tó ṣẹlẹ̀ lóru àná mọ́jú òní tí gba aṣọ lára ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn oníṣòwò inú ọjà náà
Gómìnà ìpínlẹ̀ Oǹdó lu àwọn Olóógun lọ́gọ Ẹnu:Ó ní Àwọn Ni Òpó tó di Naijiria Mú
Gómìnà ìpínlẹ̀ Oǹdó, Họnọrébù Lucky Orímisàn Aiyédàtiwa ti lu awọn ọmọ olóógun ilẹ̀ Nàìjíríà lọ́gọ ẹnu fún ipa takuntakun ti
Oníwáàsí Àgbáyé Nnì, Muhideen Àjàní Bello ti di olóògbé
Ògbóǹtarìgì Oníwáàsí Àgbáyé Nnì, Muhideen Àjàní Bello ti di olóògbé.Ohun pàtó tó fa ikú olóògbé náà kò ti fi ojú
Owó oṣù tuntun ni àwọn Òṣìṣẹ́ Ipinlẹ̀ Oǹdó yóò fi gbowó Osù kọkànlá….Ọlápàdé
Adelé alága ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Oǹdó, Ọ̀gbẹ́ni Adémọ́lá Ọlápàdé ti fi àwọn òṣìṣẹ́ ipinlẹ̀ Oǹdó lọ́kàn balẹ̀ pé
Ní Kwara,Olùkọ̀ dín dùǹdú Ìyà fún Àgùnbánirọ̀:Ó ní kò mọ̀ bí a ti ń kí Ènìyàn
Bí ẹní lu bàrà ní àwọn olùkọ mélòó kan ní ilé ẹ̀kọ́ Government Day Secondary School,Kúléndé, Ìlọrin ṣe lu Àgùnbánirọ̀
Ìpínlẹ̀ Oǹdó Ṣe Ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ Ìgbìmọ̀ Ayẹyẹ Ìrántí Àwọn Ọmọ Olóógun tó Sún lójú ìjà ti ọdún 2025
Alákóso fún ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ àwọn obìnrin ní ìpínlè Oǹdó, Díákónì Lọlá Fágbèmí ti ṣe Ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ tó máa
Nínú Sọ́ọ̀sì Níbàdàn,Olè jí Màálù tí wọ́n fẹ́ fi ṣe Ìkórè tú lọ lórí ìṣo.
Bí àlá ló ṣe rí nílé ìjọsìn ìjọ Mímọ́ Kristi láti Ọ̀run wá ìyẹn ,Celestial Church of Christ,Testimony Parish,Elerumoke,Ẹgbẹ́dá, Ìyànà
