
Nítorí rúkèrúdò òṣèlú tó tí ń mi ìpínlẹ̀ Rivers lògbòlògbò fún ìgbà pípẹ́ láàrin Gómìnà Siminalaye Fubara àti bàbá-ń-gbẹ̀jọ́ rẹ̀ tíì tún ṣe Mínísítà fún olú ìlú ilésà wa,Nyensom Wike, Ààrẹ Bọ́lá Tinúbú ti kéde Ìjọba Pàjáwìrì ni ìpínlè Rivers.
Nínú ọ̀rọ̀ tó bá gbogbo ọmọ Naijiria sọ láagó méjè ìrọ̀lẹ́ yìí lórí ẹrọ Tẹlifísàn àti Rédíò ló ti pàṣẹ ìjọba Pàjáwìrì náà.
Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn ń bá lọ́nà..

Oyè Oyèdọ̀tun jẹ́ gbajúgbajà Agbóhùnsáfẹ́fẹ́ Oníròyìn,Akéwì,Olórin,Ọ̀ǹkọ̀wé, àti Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn.Ìfẹ́ rẹ̀ sí iṣẹ́ ìròyìn àti èdè Yorùbá ló fa ìdásílẹ̀ ìkànnì yìí.A ti fi ìkòkò ṣe ọbẹ̀,ó yá ẹ je ká tọ́ ọ wò..Oyinmọmọ!
