Ẹ bẹ̀rẹ̀ ìjíròrò lórí Owó oṣù tuntun fún Àwọn Òṣìṣẹ́….Àjọ Àwọn Òṣìṣẹ́
Àjọ àwọn òṣìṣẹ́ nilẹ̀ wa ti ṣín àjọ tó ń bá ìjọba ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan jíròrò lórí owó oṣù tuntun ní […]
Àjọ àwọn òṣìṣẹ́ nilẹ̀ wa ti ṣín àjọ tó ń bá ìjọba ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan jíròrò lórí owó oṣù tuntun ní […]
Hmmm! Ikú ti gbẹ̀mí ìyàwó Gómìnà ìpínlẹ̀ Akwa Ibom, Arábìnrin Patience Umo Eno.Àná ọjọ́ ọjóbọ ni Arábìnrin ọ̀hún jẹ́ ìpè
Àjọ eleto idibo nipinle Ondo tí a mọ̀ sí ODIEC ti bèrè itanijí ohun ìlánilọ́yẹ̀ fún àwọn olóṣèlú ní ìgbáradì
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn Mínísítà ìjọba àpapọ̀ ni jìnnìjìnnì ti mú nitori ìròyìn tó ń tàn kiri pe Ààrẹ Bọ́lá Tinúbú
Olùkọ́ àgbà Yunifásítì kan, tíí tún ṣe Olórí ẹ̀ka tó ń kọ́ni ní ìmọ̀ nípa ọ̀rọ̀ òṣèlú nílé ẹ̀kọ́ gíga
Àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Edo ti dìbò yan Gómìnà tuntun ti yóò máa ṣe àkóṣo ipinle náà fún ọdún mẹ́rin miiran.Onítọ̀hún
Bámúbámú ni gbogbo ọ̀nà igboro ìlú Lokoja kún fún àwọn olùfẹ̀hónú hàn tí gbogbo wọn gbé pátákó Ajúwe tó ń
Bí-ó- tilẹ̀-jẹ́-pé àjọ INEC kò tíì sọ ẹni tó wọlé yanya ninu ètò ìdìbò sí ipò Gómìnà ìpínlẹ̀ Edo, ṣùgbọ́n
Oyewumi OyedotunOyè Oyèdọ̀tun jẹ́ gbajúgbajà Agbóhùnsáfẹ́fẹ́ Oníròyìn,Akéwì,Olórin,Ọ̀ǹkọ̀wé, àti Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn.Ìfẹ́ rẹ̀ sí iṣẹ́ ìròyìn àti èdè Yorùbá ló fa ìdásílẹ̀