Láìka àṣẹ ilé-ẹjọ́ sí ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ wáyé ni ìpínlẹ̀ Rivers

Àṣẹ ilé ẹjọ

Ètò ìdìbò sí ipò Alága ìjọba ìbílẹ̀ àti àwọn kánsílọ̀ ló ti wáyé yíká ipinle Rivers loni-in.

Bí-ó-tilẹ̀-jẹ́-pé ìdájọ́ ilé ẹjọ gíga kan ni ìlú Abuja kò fara mó bí ètò ìdìbò náà ṣe wáyé.

Ohun tí ó fa jágbánrúju ni rúkèrúdò tó ń wáyé láàrin Gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers ,Fubara àti Babańgbẹ̀jọ́ọ rẹ̀, ìyẹn Mínísítà fún olú ìlú wa Nyesom  Wike .

Ètò Òṣèlú ìpínlè Rivers lohun tí àwọn oníròyìn n jẹ lẹ́nu bí ẹní jẹ gúgúrú lẹ́nu lọ́ọ́lọ́ọ́ yìí.

Leave a Comment

Your email address will not be published. Required fields are marked *

Scroll to Top
×